Grace and Truth

This website is under construction !

Search in "Yoruba":
Home -- Yoruba -- 20-For Readers of the Qur'an -- 086 (Who is The Greatest?)
This page in: -- Arabic? -- English -- French? -- Hausa -- Igbo -- Indonesian -- Somali -- YORUBA

Previous Chapter -- Next Chapter

20. Fun awon Oluka Kurani
IWE 6 - ṢE O MỌ OGBON KRISTI?

27. Tani O tobi julo?


1 Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ Jesu wá, wọ́n ní, “Ta ni ó tóbi jùlọ ní ìjọba ọ̀run? 2 omode si ara Re, o si gbe e siwaju won, 3 o si wipe, Lõtọ ni mo wi fun nyin, Bikoṣepe ẹnyin ba yipada, ti ẹ si dabi ọmọ, ẹnyin kì yio wọ̀ ijọba ọrun. 4 Ẹnikẹ́ni tí ó bá rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọmọ kékeré yìí, òun ni ẹni tí ó tóbi jùlọ ní ìjọba ọ̀run. 5 Ẹnikẹ́ni tí ó bá sì gba irú ọmọ bẹ́ẹ̀ ní orúkọ mi gbà mí.” (Mátíù 18:1-5)

25 Ṣùgbọ́n Jésù pè wọ́n sọ́dọ̀ ara rẹ̀, ó sì wí pé, ‘Ẹ̀yin mọ̀ pé àwọn olórí àwọn aláìkọlà a máa jẹ olúwa lé wọn lórí, àwọn ènìyàn ńlá wọn a sì máa lo ọlá àṣẹ lórí wọn. 26 Kò rí bẹ́ẹ̀ láàárín yín, ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ di ẹni ńlá láàárín yín yóò jẹ́ ìránṣẹ́ yín, 27 àti ẹnikẹ́ni tí ó bá sì fẹ́ jẹ́ àkọ́kọ́ nínú yín yóò jẹ́ ẹrú yín; 28 nítorí Ọmọ ènìyàn kò wá láti ṣe ìránṣẹ́, bí kò ṣe láti sìn, àti láti fi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìràpadà fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn.” (Mátíù 20:25-28)

13 Nigbana ni a mu awon omode kan wa sodo Re ki O le gbe owo le won, ki o si gbadura; àwọn ọmọ-ẹ̀yìn sì bá wọn wí. 14 Ṣugbọn Jesu wipe, Ẹ jọwọ awọn ọmọ lọwọ, má si ṣe di wọn lọwọ lati wá sọdọ mi; nítorí irú àwọn wọ̀nyí ni ìjọba ọ̀run.’ 15 Nígbà tí ó sì gbé ọwọ́ lé wọn, ó kúrò níbẹ̀.” (Mátíù 19:13-15)

www.Grace-and-Truth.net

Page last modified on October 11, 2024, at 12:31 PM | powered by PmWiki (pmwiki-2.3.3)